Haruna Iṣọ́lá àti Ẹgbẹ́ Majority ìlú Cotonou?
Ta lo mọ nkan ti o ṣelẹ́ si ẹgbẹ́ ọmọ Yorùbá ti o wà ni Cotonou – “Ẹgbẹ́ Majority“, ti Bàbá Haruna Iṣọ́lá fi kọrin ni ọdún 1982 nínú àwo (orin) ti wọn pe ní “Ẹgbẹ́ Ọrẹdẹgbẹ́, Kaduna”?
Ṣe Ẹgbẹ́ Majority ṣi wà ni ìlú Cotonou, ni orílẹ̀-ede Benin, lóni?
